12 Obìnrin náà wá sọ pé: “Bí Jèhófà Ọlọ́run rẹ ti wà láàyè, mi ò ní búrẹ́dì kankan, àfi ẹ̀kúnwọ́ ìyẹ̀fun nínú ìkòkò àti òróró díẹ̀ nínú ìṣà kékeré.+ Ńṣe ni mò ń ṣa igi díẹ̀ jọ, kí n lè wọlé lọ ṣe nǹkan díẹ̀ fún èmi àti ọmọ mi. Lẹ́yìn tí a bá ti jẹ ẹ́ tán, a ò ní nǹkan míì, ikú ló kàn.”