5 Àwọn èèyàn Jerúsálẹ́mù àti gbogbo Jùdíà àti gbogbo ìgbèríko tó yí Jọ́dánì ká máa ń lọ sọ́dọ̀ rẹ̀,+6 ó ń ṣèrìbọmi* fún wọn ní odò Jọ́dánì,+ wọ́n sì ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn ní gbangba.
20 Hẹ́rọ́dù bẹ̀rù Jòhánù, ó mọ̀ pé olódodo ni, èèyàn mímọ́ sì ni,+ torí náà, ó ń dáàbò bò ó. Lẹ́yìn tó gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, kò mọ ohun tó máa ṣe rárá, síbẹ̀ tayọ̀tayọ̀ ló máa ń gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.