ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè

  • Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
  • Ojú Ìwé Tí Wọ́n Kọ Àkọlé Sí/Ojú Ìwé Tí Wọ́n Kọ Orúkọ Òǹṣèwé Sí
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
  • APÁ 1
    • APÁ 1
      Kí Jésù Tó Bẹ̀rẹ̀ Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Rẹ̀
    • ORÍ 1
      Ìkéde Méjì Látọ̀dọ̀ Ọlọ́run
    • ORÍ 2
      Wọ́n Pọ́n Jésù Lé Kí Wọ́n Tó Bí I
    • ORÍ 3
      Wọ́n Bí Ẹni Tó Máa Ṣètò Ọ̀nà Sílẹ̀
    • ORÍ 4
      Màríà Lóyún Láìṣègbéyàwó
    • ORÍ 5
      Ìgbà Wo Ni Wọ́n Bí Jésù, Ibo sì Ni Wọ́n Bí I Sí?
    • ORÍ 6
      Ọmọ Tí Ọlọ́run Ṣèlérí
    • ORÍ 7
      Àwọn Awòràwọ̀ Wá Sọ́dọ̀ Jésù
    • ORÍ 8
      Wọ́n Sá Lọ Mọ́ Ọba Burúkú Kan Lọ́wọ́
    • ORÍ 9
      Ó Ń Dàgbà ní Násárẹ́tì
    • ORÍ 10
      Jósẹ́fù àti Ìdílé Rẹ̀ Rìnrìn Àjò Lọ sí Jerúsálẹ́mù
    • ORÍ 11
      Jòhánù Arinibọmi Ṣètò Ọ̀nà Sílẹ̀
  • APÁ 2
    • APÁ 2
      Ìbẹ̀rẹ̀ Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Jésù
    • ORÍ 12
      Jésù Ṣe Ìrìbọmi
    • ORÍ 13
      Kẹ́kọ̀ọ́ Látinú Bí Jésù Ṣe Kojú Àdánwò
    • ORÍ 14
      Jésù Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Ní Ọmọ Ẹ̀yìn
    • ORÍ 15
      Jésù Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu Àkọ́kọ́
    • ORÍ 16
      Jésù Ní Ìtara Fún Ìjọsìn Tòótọ́
    • ORÍ 17
      Jésù Kọ́ Nikodémù Lẹ́kọ̀ọ́ ní Òru
    • ORÍ 18
      Jòhánù Ń Dín Kù, Àmọ́ Jésù Ń Pọ̀ Sí I
    • ORÍ 19
      Jésù Kọ́ Obìnrin Ará Samáríà Kan Lẹ́kọ̀ọ́
  • APÁ 3
    • APÁ 3
      Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Tó Ta Yọ Tí Jésù Ṣe ní Gálílì
    • ORÍ 20
      Iṣẹ́ Ìyanu Kejì ní Kánà
    • ORÍ 21
      Jésù Lọ sí Sínágọ́gù Tó Wà ní Násárẹ́tì
    • ORÍ 22
      Àwọn Ọmọ Ẹ̀yìn Mẹ́rin Di Apẹja Èèyàn
    • ORÍ 23
      Jésù Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu ní Kápánáúmù
    • ORÍ 24
      Jésù Mú Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Rẹ̀ Gbòòrò Sí I ní Gálílì
    • ORÍ 25
      Jésù Fàánú Hàn sí Adẹ́tẹ̀ Kan, Ó sì Wò Ó Sàn
    • ORÍ 26
      “A Dárí Àwọn Ẹ̀ṣẹ̀ Rẹ Jì Ọ́”
    • ORÍ 27
      Jésù Pe Mátíù
    • ORÍ 28
      Kí Nìdí Tí Àwọn Ọmọlẹ́yìn Jésù Kò Fi Gbààwẹ̀?
    • ORÍ 29
      Ṣé Èèyàn Lè Ṣe Ohun Tó Dáa Lọ́jọ́ Sábáàtì?
    • ORÍ 30
      Bí Jésù Ṣe Jẹ́ sí Baba Rẹ̀
    • ORÍ 31
      Wọ́n Já Ọkà Jẹ Lọ́jọ́ Sábáàtì
    • ORÍ 32
      Kí Ló Bófin Mu ní Sábáàtì?
    • ORÍ 33
      Jésù Mú Àsọtẹ́lẹ̀ Àìsáyà Ṣẹ
    • ORÍ 34
      Jésù Yan Àwọn Àpọ́sítélì Méjìlá
    • ORÍ 35
      Ìwàásù Orí Òkè
    • ORÍ 36
      Ọ̀gágun Kan Fi Hàn Pé Òun Nígbàgbọ́ Tó Lágbára
    • ORÍ 37
      Jésù Jí Ọmọ Opó Kan Dìde
    • ORÍ 38
      Jòhánù Fẹ́ Gbọ́rọ̀ Látẹnu Jésù
    • ORÍ 39
      Jésù Dẹ́bi fún Ìran Aláìgbọràn
    • ORÍ 40
      Ẹ̀kọ́ Nípa Ìdáríjì
    • ORÍ 41
      Agbára Wo Ni Jésù Fi Ń Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu?
    • ORÍ 42
      Jésù Bá Àwọn Farisí Wí
    • ORÍ 43
      Àwọn Àpèjúwe Nípa Ìjọba Ọlọ́run
    • ORÍ 44
      Jésù Mú Kí Ìjì Dáwọ́ Dúró Lórí Òkun
    • ORÍ 45
      Agbára Jésù Ju Ti Àwọn Ẹ̀mí Èṣù Lọ
    • ORÍ 46
      Obìnrin Kan Rí Ìwòsàn Nígbà Tó Fọwọ́ Kan Aṣọ Jésù
    • ORÍ 47
      Jésù Jí Ọmọbìnrin Kan Dìde!
    • ORÍ 48
      Jésù Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu, Àmọ́ Àwọn Ará Násárẹ́tì Kò Gbà Á Gbọ́
    • ORÍ 49
      Ó Wàásù, Ó sì Dá Àwọn Àpọ́sítélì Lẹ́kọ̀ọ́ ní Gálílì
    • ORÍ 50
      Wọ́n Ṣe Tán Láti Wàásù Láìka Àtakò Sí
    • ORÍ 51
      Wọ́n Pa Èèyàn Níbi Ayẹyẹ Ọjọ́ Ìbí Kan
    • ORÍ 52
      Ó Fi Ìwọ̀nba Búrẹ́dì àti Ẹja Bọ́ Ẹgbẹẹgbẹ̀rún Èèyàn
    • ORÍ 53
      Alákòóso Kan Tó Láṣẹ Lórí Àwọn Nǹkan Àdáyébá
    • ORÍ 54
      Jésù “Ni Oúnjẹ Ìyè”
    • ORÍ 55
      Ọ̀rọ̀ Jésù Ya Ọ̀pọ̀ Èèyàn Lẹ́nu
    • ORÍ 56
      Kí Ló Ń Sọni Di Aláìmọ́?
    • ORÍ 57
      Jésù Wo Ọmọbìnrin Kan àti Adití Kan Sàn
    • ORÍ 58
      Ó Mú Kí Búrẹ́dì Pọ̀, Ó sì Kìlọ̀ Nípa Ìwúkàrà
    • ORÍ 59
      Ta Ni Ọmọ Èèyàn?
    • ORÍ 60
      Ìran Ìyípadà Ológo
    • ORÍ 61
      Jésù Wo Ọmọkùnrin Tí Ẹ̀mí Èṣù Ń Yọ Lẹ́nu Sàn
    • ORÍ 62
      Ẹ̀kọ́ Pàtàkì Nípa Ẹ̀mí Ìrẹ̀lẹ̀
    • ORÍ 63
      Méjì Lára Ìmọ̀ràn Jésù
    • ORÍ 64
      Ìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Dárí Jini
    • ORÍ 65
      Jésù Ń Kóni Nígbà Tó Ń Lọ sí Jerúsálẹ́mù
  • APÁ 4
    • APÁ 4
      Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Tí Jésù Pa Dà Ṣe ní Jùdíà
    • ORÍ 66
      Jésù Lọ sí Jerúsálẹ́mù Nígbà Àjọyọ̀ Àwọn Àgọ́ Ìjọsìn
    • ORÍ 67
      “Èèyàn Kankan Ò Sọ̀rọ̀ Báyìí Rí”
    • ORÍ 68
      Ọmọ Ọlọ́run Ni “Ìmọ́lẹ̀ Ayé”
    • ORÍ 69
      Ṣé Ábúráhámù Ni Bàbá Wọn Àbí Èṣù?
    • ORÍ 70
      Jésù La Ojú Ọkùnrin Kan Tí Wọ́n Bí Ní Afọ́jú
    • ORÍ 71
      Àwọn Farisí Gbọ́ Tẹnu Ọkùnrin Afọ́jú Náà
    • ORÍ 72
      Jésù Rán Àádọ́rin (70) Ọmọ Ẹ̀yìn Jáde Lọ Wàásù
    • ORÍ 73
      Ará Samáríà Kan Fi Hàn Pé Òun Láàánú
    • ORÍ 74
      Ẹ̀kọ́ Nípa Aájò Àlejò àti Àdúrà
    • ORÍ 75
      Jésù Sọ Ohun Tó Ń Fúnni Láyọ̀
    • ORÍ 76
      Farisí Kan Gba Jésù Lálejò
    • ORÍ 77
      Jésù Sọ̀rọ̀ Nípa Ọrọ̀
    • ORÍ 78
      Jésù Ní Kí Ìríjú Olóòótọ́ Náà Múra Sílẹ̀
    • ORÍ 79
      Ìdí Táwọn Èèyàn Náà Fi Máa Pa Run
    • ORÍ 80
      Olùṣọ́ Àgùntàn Àtàtà àti Agbo Àgùntàn
    • ORÍ 81
      Ọ̀kan Ni Jésù àti Baba, Àmọ́ Jésù Kì Í Ṣe Ọlọ́run
  • APÁ 5
    • APÁ 5
      Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Tí Jésù Pa Dà Ṣe ní Ìlà Oòrùn Jọ́dánì
    • ORÍ 82
      Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Jésù ní Pèríà
    • ORÍ 83
      Àwọn Tí Ọlọ́run Pè Síbi Àsè Kan
    • ORÍ 84
      Iṣẹ́ Kékeré Kọ́ Lẹnì Kan Máa Ṣe Kó Tó Lè Di Ọmọ Ẹ̀yìn
    • ORÍ 85
      Àwọn Áńgẹ́lì Máa Ń Yọ̀ Tí Ẹlẹ́ṣẹ̀ Kan Bá Ronú Pìwà Dà
    • ORÍ 86
      Ọmọ Tó Sọ Nù Pa Dà Wálé
    • ORÍ 87
      Múra Sílẹ̀, Kó O sì Jẹ́ Ọlọ́gbọ́n
    • ORÍ 88
      Nǹkan Yí Pa Dà fún Ọkùnrin Ọlọ́rọ̀ Kan àti Lásárù
    • ORÍ 89
      Ó ń kọ́ni ní Pèríà bó ṣe ń lọ sí Jùdíà
    • ORÍ 90
      “Àjíǹde àti Ìyè”
    • ORÍ 91
      Jésù Jí Lásárù Dìde
    • ORÍ 92
      Jésù Wo Adẹ́tẹ̀ Mẹ́wàá Sàn, Ọ̀kan Pa Dà Wá Dúpẹ́
    • ORÍ 93
      Ọlọ́run Máa Ṣí Ọmọ Èèyàn Payá
    • ORÍ 94
      Ohun Méjì Tó Ṣe Pàtàkì—Àdúrà àti Ẹ̀mí Ìrẹ̀lẹ̀
    • ORÍ 95
      Jésù Sọ̀rọ̀ Nípa Ìkọ̀sílẹ̀, Ó sì Fìfẹ́ Hàn Sáwọn Ọmọdé
    • ORÍ 96
      Jésù Dáhùn Ìbéèrè Ọ̀dọ́kùnrin Ọlọ́rọ̀ Kan
    • ORÍ 97
      Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà Àjàrà
    • ORÍ 98
      Àwọn Àpọ́sítélì Tún Ń Wá Ipò Ọlá
    • ORÍ 99
      Jésù La Ojú Àwọn Afọ́jú, Ó sì Ran Sákéù Lọ́wọ́
    • ORÍ 100
      Àpèjúwe Mínà Mẹ́wàá
  • APÁ 6
    • APÁ 6
      Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Tí Jésù Ṣe Kẹ́yìn
    • ORÍ 101
      Wọ́n Lọ Jẹun Nílé Símónì ní Bẹ́tánì
    • 102
      Ọba Gun Ọmọ Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Wọ Jerúsálẹ́mù
    • ORÍ 103
      Jésù Fọ Tẹ́ńpìlì Mọ́ Lẹ́ẹ̀kan Sí I
    • ORÍ 104
      Lẹ́yìn Táwọn Júù Gbọ́ Ohùn Ọlọ́run, Ṣé Wọ́n Gba Jésù Gbọ́?
    • ORÍ 105
      Jésù Fi Igi Ọ̀pọ̀tọ́ Kan Kọ́ Wọn Lẹ́kọ̀ọ́ Nípa Ìgbàgbọ́
    • ORÍ 106
      Àpèjúwe Méjì Nípa Ọgbà Àjàrà
    • ORÍ 107
      Ọba Kan Pe Àwọn Èèyàn Wá Síbi Ayẹyẹ Ìgbéyàwó
    • ORÍ 108
      Ìdáhùn Jésù Ò Jẹ́ Káwọn Ọ̀tá Rẹ̀ Rí I Mú
    • ORÍ 109
      Ó Dẹ́bi Fáwọn Aṣáájú Ìsìn Tó Ń Ta Kò Ó
    • ORÍ 110
      Ọjọ́ Tí Jésù Wá sí Tẹ́ńpìlì Kẹ́yìn
    • ORÍ 111
      Àwọn Àpọ́sítélì Ní Kí Jésù Fún Àwọn Ní Àmì
    • ORÍ 112
      Ẹ̀kọ́ Tí Àpèjúwe Wúńdíá Mẹ́wàá Kọ́ Wa
    • ORÍ 113
      Ẹ̀kọ́ Tí Àpèjúwe Tálẹ́ńtì Kọ́ Wa
    • ORÍ 114
      Kristi Ṣèdájọ́ Àgùntàn àti Ewúrẹ́
    • ORÍ 115
      Ìrékọjá Tí Jésù Máa Ṣe Kẹ́yìn Ń Sún Mọ́lé
    • ORÍ 116
      Jésù Kọ́ Wọn Lẹ́mìí Ìrẹ̀lẹ̀ Níbi Ìrékọjá Tó Ṣe Kẹ́yìn
    • ORÍ 117
      Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa
    • ORÍ 118
      Wọ́n Jiyàn Nípa Ẹni Tó Tóbi Jù
    • ORÍ 119
      Jésù Ni Ọ̀nà, Òtítọ́ àti Ìyè
    • ORÍ 120
      Béèyàn Ṣe Lè Dà Bí Ẹ̀ka Tó Ń So Èso, Kó sì Di Ọ̀rẹ́ Jésù
    • ORÍ 121
      “Ẹ Mọ́kàn Le! Mo Ti Ṣẹ́gun Ayé”
    • ORÍ 122
      Àdúrà Tí Jésù Gbà Kẹ́yìn ní Yàrá Tó Wà Lókè
    • ORÍ 123
      Jésù Gbàdúrà Nígbà Tí Ẹ̀dùn Ọkàn Bá A
    • ORÍ 124
      Júdásì Da Jésù, Wọ́n sì Fàṣẹ Ọba Mú Jésù
    • ORÍ 125
      Wọ́n Mú Jésù Lọ Sọ́dọ̀ Ánásì àti Káyáfà
    • ORÍ 126
      Pétérù Sẹ́ Jésù Nílé Káyáfà
    • ORÍ 127
      Jésù Jẹ́jọ́ Níwájú Sàhẹ́ndìrìn àti Pílátù
    • ORÍ 128
      Pílátù àti Hẹ́rọ́dù Rí I Pé Jésù Ò Jẹ̀bi
    • ORÍ 129
      Pílátù Sọ Pé: “Ẹ Wò Ó! Ọkùnrin Náà Nìyí!”
    • ORÍ 130
      Ó Fa Jésù Lé Wọn Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Lọ Pa Á
    • ORÍ 131
      Ọba Kan Ń Jìyà Láìṣẹ̀ Lórí Òpó Igi
    • ORÍ 132
      “Ó Dájú Pé Ọmọ Ọlọ́run Ni Ọkùnrin Yìí”
    • ORÍ 133
      Wọ́n Ṣètò Òkú Jésù, Wọ́n sì Lọ Sin Ín
    • ORÍ 134
      Ọlọ́run Ti Jí Jésù Dìde, Ibojì Rẹ̀ sì Ti Ṣófo!
    • ORÍ 135
      Jésù Fara Han Ọ̀pọ̀ Èèyàn Lẹ́yìn Tó Jíǹde
    • ORÍ 136
      Ohun Tó Ṣẹlẹ̀ Létíkun Gálílì
    • ORÍ 137
      Ọ̀pọ̀ Èèyàn Ló Rí Jésù Ṣáájú Ọjọ́ Pẹ́ńtíkọ́sì
    • ORÍ 138
      Kristi Wà Lọ́wọ́ Ọ̀tún Ọlọ́run
    • ORÍ 139
      Jésù Parí Iṣẹ́ Rẹ̀, Ó sì Máa Sọ Ayé Di Párádísè
  • Tó O Bá Fẹ́ Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jésù, Ó Yẹ Kó O . . .
  • Atọ́ka Ẹsẹ Ìwé Mímọ́
  • Atọ́ka Àwọn Àpèjúwe (Àkàwé)
  • Àwọn Àsọtẹ́lẹ̀ Kan Nípa Mèsáyà
  • Àwọn Ibi Tí Jésù Gbé Tó sì Ti Kọ́ni
Yorùbá Publications (1987-2026)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2026 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́